a
Mt 27.27-31
;
Mk 15.16-20
;
Lk 22.63-65
;
23.11
.
John 19:2-3
2
a
Àwọn ọmọ-ogun sì hun adé ẹ̀gún, wọ́n sì fi dé e ní orí, wọ́n sì fi aṣọ ìgúnwà elése àlùkò wọ̀ ọ́.
3
Wọ́n sì wí pé, “Kábíyèsí, ọba àwọn Júù!” Wọ́n sì fi ọwọ́ wọn gbá a ní ojú.
Copyright information for
YorBMYO